Abubakar Tafawa Balewa
Olóṣèlú
(Àtúnjúwe láti Tafawa Balewa)
Abubakar Tafawa Balewa (December 1912 – January 15, 1966) je omo orile ede Nàìjíríà, lati apa ariwa ile Nàìjíríà[1]. Balewa je Alakoso Agba (prime minister) akoko fun ile Nàìjíríà ni Igba Oselu Akoko ile Nàìjíríà leyin igba ti Nàìjíríà gba ominira ni odun 1960.[2] Eni ayesi ni kariaye, o gba owo ni orile Afrika gege bi ikan lara awon ti won daba idasile Akojoegbe Okan ara Afrika (Organization of African Unity, OAU)[3].[4][5]
Abubakar Tafawa Balewa | |
---|---|
Alakoso Agba ile Nàìjíríà | |
In office October 1, 1959 – January 15, 1966 | |
Arọ́pò | None |
Àwọn àlàyé onítòhún | |
Ọjọ́ìbí | 1912 Bauchi, Nàìjíríà |
Aláìsí | 15 January, 1966 |
Ẹgbẹ́ olóṣèlú | Northern People's Congress |
Igba ewe ati ise-owo
Àyọkà yìí tàbí apá rẹ̀ únfẹ́ àtúnṣe sí. Ẹ le fẹ̀ jù báyìí lọ tàbí kí ẹ ṣàtúnṣe rẹ̀ lọ́nà tí yíò mu kúnrẹ́rẹ́. Ẹ ran Wikipedia lọ́wọ́ láti fẹ̀ẹ́ jù báyìí lọ. |
Itokasi
Wikimedia Commons ní àwọn amóunmáwòrán bíbátan mọ́: Abubakar Tafawa Balewa |
🔥 Top keywords: Ojúewé Àkọ́kọ́Ọ̀rọ̀-Orúkọ (Èdè Yorùbá)Pàtàkì:SearchEre idarayaÀsà oge ṣíṣẹ́ ní ilè yorùbáIṣẹ́ Àgbẹ̀Ogun Àgbáyé Ẹlẹ́ẹ̀kejìÀṣà YorùbáÀṣà Ìsọmọ-lórúkọ nílẹ̀ YorùbáÒgún LákáayéWikipedia:Nípa WikipediaWikipediaOwe YorubaAkanlo-edeỌrọ orúkọOrúkọ YorùbáWikipedia:Èbúté ÀwùjọHóséà Ayoola AgboolaÈdè YorùbáPàtàkì:ÀwọnÀtúnṣeTuntunWikipedia:Abẹ́ igiÀjàkálẹ̀ àrùn COVID-19 ní ilẹ̀ NàìjíríàỌbáfẹ́mi Awólọ́wọ̀Wikipedia:Àwọn àyọkà kúkúrúFáwẹ̀lì YorùbáÒrò àyálò YorùbáGbólóhùn YorùbáÀwọn Ọba Ilẹ̀ YorùbáAṣọHerbert MacaulayMọ́remí ÁjàṣoroṢàngóOmiEwìItan Ijapa ati AjaÀrokòAustrálíàIlẹ̀ọba Aṣọ̀kanAgbègbè Ìjọba Ìbílẹ̀ Àríwá Yewa